Numbers 22:23
23
Nígbà tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà sì rí angẹli
Olúwa
tí ó dúró ní ojú ọ̀nà pẹ̀lú idà tí a fàyọ ní ọwọ́ rẹ̀, ó kọjú kúrò ní ọ̀nà lọ sínú oko. Balaamu sì lù ú pé kí ó gbé òhun padà lọ sí ojú ọ̀nà.
Copyright information for
YorBMYO